×
Image

Àwọn Sunnah Ànábì - (Èdè Yorùbá)

Èyí, nínú ìran rẹ̀, ni àkọ́kọ́ àkànṣe iṣẹ́ orí ẹ̀rọ-ayélujára, tó ní í ṣe pẹ̀lú ìmọ̀ ẹ̀rọ, èyí tó ní àkàkún pẹ̀lú ìlànà afaraṣe Ànábì – kí ìkẹ́ àti ọlà Ọlọ́hun máa bá a – àti àwọn ìrántí Ọlọ́hun tí ó máa ń ṣe ní ojoojúmọ́. Ó ń bá gbogbo....